Sekariah 8:14 OYCB

[14] Nítorí báyìí ni OLÚWA àwọn ọmọ-ogun wí: “Gẹ́gẹ́ bí mo ti rò láti ṣe yín níbi nígbà tí àwọn baba yín mú mi bínú,” ni OLÚWA àwọn ọmọ-ogun wí, tí èmi kò sì ronúpìwàdà.

About this translation

Life Bible app icon
Get the Life Bible app Read offline, sync highlights and notes, and study with your library on any device.