Sekariah 1:3 OYCB

[3] Nítorí náà sọ fún àwọn ènìyàn. Èyí ni ohun tí OLÚWA àwọn ọmọ-ogun wí: ‘Ẹ padà sí ọ̀dọ̀ mi,’ báyìí ní OLÚWA àwọn ọmọ-ogun wí, ‘èmi náà yóò sì padà sí ọ̀dọ̀ yín,’ ni OLÚWA àwọn ọmọ-ogun wí.

About this translation

Life Bible app icon
Get the Life Bible app Read offline, sync highlights and notes, and study with your library on any device.