Saamu 77:2 OYCB

[2] Nígbà tí mo wà nínú ìpọ́njú, mo wá OLÚWA; ní òru ni mo na ọwọ́ mi jáde ní àìkáárẹ̀ ọkàn mí sì kọ̀ láti tù ú nínú.

About this translation

Life Bible app icon
Get the Life Bible app Read offline, sync highlights and notes, and study with your library on any device.