Rutu 2:4 OYCB

[4] Nígbà náà ni Boasi dé láti Bẹtilẹhẹmu tí ó sì kí àwọn olùkórè wí pé, “Kí OLÚWA wà pẹ̀lú yín.” Wọ́n sì dá a lóhùn pé, “Kí OLÚWA bùkún fún ọ.”

About this translation

Life Bible app icon
Get the Life Bible app Read offline, sync highlights and notes, and study with your library on any device.