Numeri 11:1 OYCB

[1] Àwọn ènìyàn ń ṣe àròyé nípa wàhálà wọn sí etí ìgbọ́ OLÚWA. Ìbínú OLÚWA sì ru sókè nígbà tí ó gbọ́ àròyé yìí. Nígbà náà ni iná jáde láti ọ̀dọ̀ OLÚWA bọ́ sí àárín wọn, ó sì run àwọn tó wà ní òpin ibùdó.

About this translation

Life Bible app icon
Get the Life Bible app Read offline, sync highlights and notes, and study with your library on any device.