Jeremiah 50:31 OYCB

[31] “Wò ó, èmi yóò dojú kọ ọ́ ìwọ agbéraga,” ni Olúwa, OLÚWA àwọn ọmọ-ogun wí, “nítorí ọjọ́ rẹ ti dé, àkókò tí èmi ó bẹ̀ ọ wò.

About this translation

Life Bible app icon
Get the Life Bible app Read offline, sync highlights and notes, and study with your library on any device.