Jeremiah 42:5 OYCB

[5] Nígbà náà ni wọ́n sọ fún Jeremiah wí pé, “Kí OLÚWA ṣe ẹlẹ́rìí òtítọ́ àti òdodo láàrín wa, bí àwa kò bá ṣe gẹ́gẹ́ bí gbogbo ohun tí OLÚWA Ọlọ́run rẹ bá rán ọ láti sọ fún wa.

About this translation

Life Bible app icon
Get the Life Bible app Read offline, sync highlights and notes, and study with your library on any device.