Jeremiah 36:7 OYCB

[7] Ó lè jẹ́ pé, ẹ̀bẹ̀ wọn yóò wá sí iwájú OLÚWA, wọ́n ó sì yípadà kúrò ní ọ̀nà búburú wọn; nítorí pé títóbi ni ìbínú àti ìrunú tí OLÚWA ti sọ sí àwọn ènìyàn yìí.”

About this translation

Life Bible app icon
Get the Life Bible app Read offline, sync highlights and notes, and study with your library on any device.