Jeremiah 31:16 OYCB

[16] Báyìí ni OLÚWA wí: “Dá ohùn rẹ dúró nínú ẹkún àti ojú rẹ nínú omijé; nítorí a ó fi èrè sí iṣẹ́ rẹ,” ni OLÚWA wí. “Wọn ó sì padà wá láti ilẹ̀ ọ̀tá.

About this translation

Life Bible app icon
Get the Life Bible app Read offline, sync highlights and notes, and study with your library on any device.