Jeremiah 16:14 OYCB

[14] “Nítorí náà, ọjọ́ náà ń bọ̀ wá,” ni OLÚWA wí, “tí àwọn ènìyàn kò ní sọ pé, ‘Dájúdájú OLÚWA wà láààyè OLÚWA ń bẹ, Ẹni tí ó mú Israẹli jáde kúrò ní Ejibiti.’

About this translation

Life Bible app icon
Get the Life Bible app Read offline, sync highlights and notes, and study with your library on any device.