Isaiah 24:15 OYCB

[15] Nítorí náà ní ìlà-oòrùn ẹ fi ògo fún OLÚWA; gbé orúkọ OLÚWA ga, àní Ọlọ́run Israẹli, ní àwọn erékùṣù ti inú Òkun.

About this translation

Life Bible app icon
Get the Life Bible app ★★★★★4.8 · 216K ratings Read offline, sync highlights and notes, and study with your library on any device.