Esra 1:2 OYCB

[2] “Èyí ni ohun tí Kirusi ọba Persia wí pé: “ ‘OLÚWA, Ọlọ́run ọ̀run, ti fún mi ní gbogbo ìjọba ayé. Ó sì ti yàn mí láti kọ́ tẹmpili OLÚWA fún un ní Jerusalẹmu tí ó wà ní Juda.

About this translation

Life Bible app icon
Get the Life Bible app Read offline, sync highlights and notes, and study with your library on any device.