Eksodu 4:31 OYCB

[31] Wọ́n sì gbàgbọ́. Nígbà tí wọ́n gbọ́ pé OLÚWA ti bẹ àwọn ọmọ Israẹli wò àti pé OLÚWA ti gbọ́ nípa ìpọ́njú wọn, wọ́n tẹríba, wọ́n sì sìn ín. Ó sì ṣe àwọn iṣẹ́ àmì náà níwájú àwọn ènìyàn náà.

About this translation

Life Bible app icon
Get the Life Bible app Read offline, sync highlights and notes, and study with your library on any device.