Eksodu 29:46 OYCB

[46] Wọn yóò sì mọ̀ pé Èmi ni OLÚWA Ọlọ́run wọn, ẹni tí ó mú wọn jáde láti ilẹ̀ Ejibiti wá, nítorí kí èmi lè máa gbé àárín wọn. Èmi ni OLÚWA Ọlọ́run wọn.

About this translation

Life Bible app icon
Get the Life Bible app Read offline, sync highlights and notes, and study with your library on any device.