Eksodu 11:7 OYCB

[7] Ṣùgbọ́n láàrín àwọn ará Israẹli ajá lásán kò ní gbó àwọn ènìyàn tàbí àwọn ẹran wọn.’ Nígbà náà ni ẹ̀yin yóò mọ̀ pé OLÚWA ti fi ìyàtọ̀ sáàrín àwọn ará Ejibiti àti Israẹli.

About this translation

Life Bible app icon
Get the Life Bible app Read offline, sync highlights and notes, and study with your library on any device.