Deuteronomi 30:1 OYCB

[1] Nígbà tí gbogbo ìbùkún àti ègún wọ̀nyí tí mo ti gbé kalẹ̀ síwájú u yín bá wá sórí i yín àti tí o bá mú wọn sí àyà rẹ níbikíbi tí OLÚWA Ọlọ́run rẹ bá tú ọ ká sí láàrín àwọn orílẹ̀-èdè,

About this translation

Life Bible app icon
Get the Life Bible app Read offline, sync highlights and notes, and study with your library on any device.