Deuteronomi 1:41 OYCB

[41] Nígbà náà ni ẹ fèsì wí pé, “Àwa ti ṣẹ̀ sí OLÚWA. A ó sì gòkè lọ láti jà, gẹ́gẹ́ bí OLÚWA Ọlọ́run wa ti pàṣẹ fún wa.” Torí náà gbogbo yín ẹ mú ohun ìjà a yín, ẹ rò pé ó rọrùn láti gòkè lọ sí àwọn orílẹ̀-èdè olókè náà.

About this translation

Life Bible app icon
Get the Life Bible app Read offline, sync highlights and notes, and study with your library on any device.