2 Kronika 30:1 OYCB

[1] Hesekiah sì ránṣẹ́ sí gbogbo Israẹli àti Juda, ó sì kọ ìwé sí Efraimu àti Manase, kí wọn kí ó wá sínú ilé OLÚWA ní Jerusalẹmu láti pa àjọ ìrékọjá mọ́ sí OLÚWA Ọlọ́run Israẹli.

About this translation

Life Bible app icon
Get the Life Bible app Read offline, sync highlights and notes, and study with your library on any device.