1 Kronika 29:20 OYCB

[20] Dafidi sì sọ fún gbogbo ìjọ ènìyàn pé, “Nísinsin yìí, ẹ fi ìyìn fún OLÚWA Ọlọ́run yín.” Gbogbo ènìyàn sì fi ìyìn fún OLÚWA Ọlọ́run àwọn baba wọn, wọ́n sì tẹ orí wọn ba, wọ́n wólẹ̀ fún OLÚWA àti ọba.

About this translation

Life Bible app icon
Get the Life Bible app Read offline, sync highlights and notes, and study with your library on any device.