1 Kronika 21:18 OYCB

[18] Nígbà náà angẹli OLÚWA náà pàṣẹ fún Gadi láti sọ fún Dafidi pé, kí Dafidi kí ó gòkè lọ, kí ó sì tẹ́ pẹpẹ kan fún OLÚWA lórí ilẹ̀ ìpakà Arauna ará Jebusi.

About this translation

Life Bible app icon
Get the Life Bible app Read offline, sync highlights and notes, and study with your library on any device.